Jeremiah 31:15-16

Jeremiah 31:15-16 YCB

Èyí ni ohun tí OLúWA wí: “A gbọ́ ohùn kan ní Rama tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò. Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀; kò gbà kí wọ́n tu òun nínú, nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.” Báyìí ni OLúWA wí: “Dá ohùn rẹ dúró nínú ẹkún àti ojú rẹ nínú omijé; nítorí a ó fi èrè sí iṣẹ́ rẹ,” ni OLúWA wí. “Wọn ó sì padà wá láti ilẹ̀ ọ̀tá.