Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí o bá báwí, OLUWA, tí o sì kọ́ ní òfin rẹ, kí ó lè sinmi lọ́wọ́ ọjọ́ ìṣòro, títí tí a ó fi gbẹ́ kòtò fún eniyan burúkú. Nítorí OLUWA kò ní kọ àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀; kò ní ṣá àwọn eniyan ìní rẹ̀ tì
Kà ORIN DAFIDI 94
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: ORIN DAFIDI 94:12-14
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò