Akani sì dáhùn pé, “Òtítọ́ ni! Mo ti ṣẹ̀ sí OLúWA, Ọlọ́run Israẹli. Nǹkan tí mo ṣe nìyìí: Nígbà tí mo rí ẹ̀wù Babeli kan tí ó dára nínú ìkógun, àti igba ṣékélì fàdákà àti odindi wúrà olóṣùnwọ́n àádọ́ta ṣékélì, mo ṣe ojúkòkòrò wọn mo sì mú wọn. Mo fi wọ́n pamọ́ ní abẹ́ àgọ́ mi àti fàdákà ní abẹ́ rẹ̀.”
Kà Joṣua 7
Feti si Joṣua 7
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: Joṣua 7:20-21
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò