Gbọ́ adura mi, OLUWA; kí o sì jẹ́ kí igbe mi dé ọ̀dọ̀ rẹ. Má yọwọ́ lọ́ràn mi lọ́jọ́ ìṣòro! Dẹtí sí adura mi; kí o sì tètè dá mi lóhùn nígbà tí mo bá ké pè ọ́. Nítorí ọjọ́ ayé mi ń kọjá lọ bí èéfín, eegun mi gbóná bí iná ààrò. Ìdààmú bá ọkàn mi, mo rọ bíi koríko, tóbẹ́ẹ̀ tí mo gbàgbé láti jẹun. Nítorí igbe ìrora mi, mo rù kan eegun.
Kà ORIN DAFIDI 102
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: ORIN DAFIDI 102:1-5
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò