Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, OLúWA, kí o sì sìn mi lọ sí ọ̀nà tí ó tẹ́jú nítorí àwọn ọ̀tá mi. Má ṣe fi mí lé ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi lọ́wọ́, nítorí àwọn ẹlẹ́rìí èké ti dìde sí mi, wọ́n sì mí ìmí ìkà. Èmi ní ìgbàgbọ́ pé, èmi yóò rí ìre OLúWA ní ilẹ̀ alààyè. Dúró de OLúWA; kí ó jẹ alágbára, kí o sì mú ọkàn le àní dúró de OLúWA.
Kà Saamu 27
Feti si Saamu 27
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: Saamu 27:11-14
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò