Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà gbìyànjú gidigidi láti mú ọkọ̀ wà sí ilẹ̀: ṣùgbọ́n wọn kò lè ṣe é: nítorí tí Òkun túbọ̀ ru sí i, ó sì ja ẹ̀fúùfù líle sí wọn. Nítorí náà wọ́n kígbe sí OLúWA, wọ́n sì wí pé, “OLúWA àwa bẹ̀ ọ́, má ṣe jẹ́ kí àwa ṣègbé nítorí ẹ̀mí ọkùnrin yìí. Má sì ka ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sí wa ní ọrùn, nítorí ìwọ, OLúWA, ti ṣe bí ó ti wù ọ́.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé Jona, tí wọ́n sì sọ ọ́ sínú Òkun, Òkun sì dẹ́kun ríru rẹ̀. Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin náà bẹ̀rù OLúWA gidigidi, wọn si rú ẹbọ sí OLúWA, wọ́n sì jẹ́ ẹ̀jẹ́.
Kà Jona 1
Feti si Jona 1
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: Jona 1:13-16
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò