Nígbà tí Solomoni sì ti parí àdúrà, iná sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run ó sì jó ẹbọ sísun àti ẹbọ, ògo Ọlọ́run sì kún ilé OLúWA. Àwọn àlùfáà kò sì le wo ilé OLúWA náà nítorí pé ògo OLúWA kún un. Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli rí iná tí ó ń sọ̀kalẹ̀ àti ògo OLúWA lórí ilé OLúWA náà, wọ́n sì kúnlẹ̀ lórí eékún wọn pẹ̀lú ojú ni dídàbolẹ̀, wọ́n sì sin OLúWA, wọ́n sì fi ìyìn fún OLúWA wí pé, “Nítorí tí ó dára; àánú rẹ̀ sì dúró títí láéláé.”
Kà 2 Kronika 7
Feti si 2 Kronika 7
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: 2 Kronika 7:1-3
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò