1
Lefitiku 10:1
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Nadabu àti Abihu tí í ṣe ọmọ Aaroni sì mú àwo tùràrí kọ̀ọ̀kan, wọ́n fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀, wọ́n sì rú iná àjèjì níwájú OLúWA, èyí tó lòdì sí àṣẹ OLúWA.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Lefitiku 10:1
2
Lefitiku 10:3
Mose sì sọ fún Aaroni pé, “Ohun tí OLúWA ń sọ nípa rẹ̀ nìyìí nígbà tó wí pé “ ‘Ní àárín àwọn tó súnmọ́ mi, Èmi yóò fi ara mi hàn ní mímọ́ ojú gbogbo ènìyàn Ní a ó ti bu ọlá fún mi’ ” Aaroni sì dákẹ́.
Ṣàwárí Lefitiku 10:3
3
Lefitiku 10:2
Torí èyí iná jáde láti ọ̀dọ̀ OLúWA, ó sì jó wọn pa, wọ́n sì kú níwájú OLúWA.
Ṣàwárí Lefitiku 10:2
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò