1
JEREMAYA 29:11
Yoruba Bible
Nítorí pé mo mọ èrò tí mò ń gbà si yín, èrò alaafia ni, kì í ṣe èrò ibi. N óo mú kí ọjọ́ ọ̀la dára fun yín, n óo sì fun yín ní ìrètí.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí JEREMAYA 29:11
2
JEREMAYA 29:13
Ẹ óo wá mi, ẹ óo sì rí mi, bí ẹ bá fi tọkàntọkàn wá mi.
Ṣàwárí JEREMAYA 29:13
3
JEREMAYA 29:12
Ẹ óo ké pè mí, ẹ óo gbadura sí mi, n óo sì gbọ́ adura yín.
Ṣàwárí JEREMAYA 29:12
4
JEREMAYA 29:14
Ẹ óo rí mi, n óo dá ire yín pada, n óo ko yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè ati láti gbogbo ibi tí mo ti le yín lọ; n óo sì ko yín pada sí ibi tí mo ti le yín kúrò lọ sí ìgbèkùn. Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ṣàwárí JEREMAYA 29:14
5
JEREMAYA 29:10
“Nígbà tí aadọrin ọdún Babiloni bá pé, n óo mójú tó ọ̀rọ̀ yín, n óo mú ìlérí mi ṣẹ fun yín, n óo sì ko yín pada sí ibí yìí.
Ṣàwárí JEREMAYA 29:10
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò