1
JEREMAYA 14:22
Yoruba Bible
Ninu gbogbo àwọn ọlọrun èké tí àwọn orílẹ̀-èdè ń sìn, ǹjẹ́ ọ̀kan wà tí ó lè mú kí òjò rọ̀? Àbí ojú ọ̀run ní ń fúnrarẹ̀ rọ ọ̀wààrà òjò? OLUWA Ọlọrun wa, ṣebí ìwọ ni? Ìwọ ni a gbẹ́kẹ̀lé, nítorí ìwọ ni o ṣe gbogbo nǹkan wọnyi.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí JEREMAYA 14:22
2
JEREMAYA 14:7
Àwọn eniyan mi ké pè mí wí pé, ‘Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀ṣẹ̀ wa ń jẹ́rìí lòdì sí wa, sibẹsibẹ, nítorí orúkọ rẹ, gbà wá. Ọpọlọpọ ìgbà ni a ti pada lẹ́yìn rẹ, a ti ṣẹ̀ ọ́.
Ṣàwárí JEREMAYA 14:7
3
JEREMAYA 14:20-21
OLUWA, a mọ ìwà burúkú wa, ati ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wa, nítorí a ti ṣẹ̀ ọ́. Má ta wá nù nítorí orúkọ rẹ, má sì fi àbùkù kan ìtẹ́ rẹ tí ó lógo. Ranti majẹmu tí o bá wa dá, ranti, má sì ṣe dà á.
Ṣàwárí JEREMAYA 14:20-21
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò