Àwọn ètò kíkà ọ̀fé àti àyọkà tó ní ṣe pẹ̀lú Gẹn 1:26

ÈRÈDÍ Ìfojú-ìhìnrere wo ìwé Jeremiah
3 Awọn ọjọ
Gbogbo olùpèsè-ọjà ló ní èrèdí fún pípèsè ọjà kọ̀ọ̀kan. Ọlọrun dá ẹnìkọ̀ọ̀kan fún ètò àti ìlànà pàtàkì kan. Èrèdí ìgbélé-ayé ni kí á rí i dájú pé a gbé ìgbésí ayé wa láti jẹ́ kí èrèdí yìí wá sí ìmúṣẹ. Ẹkọ yìí dù láti wa àwàjinlẹ̀ lórí kókó-ọ̀rọ̀ náà.

Níní Ìrírí Ìbádọ́ọ̀rẹ́ Pẹ̀lú Ọlọ́run
Ọjọ́ Márùn-ún
Sé ò n la àkókò aginjù kọjá, láì rí omi tàbí sẹ́lẹ̀rú fún ọkàn rẹ? Báwo ni ìbá ṣe rí tí àsìkò yìí bá ní ìrètí tí ó ga jù lọ: nípasẹ mímọ Ọlọ́run jinlẹ̀, ni ògidì ati tọkàntọkàn? Ètò yìí ń gba'ni ní ìyànjú pé àkọ́kọ̀ yìí kìí ṣe lásán bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ ìgbà ni ọ rò pé o kò tẹ̀ sí iwájú. Nítorí pé kò sí ọ̀nà tí ò kò báa rìn, Ọlọ́run n rìn pẹ̀lú rẹ gẹ́gẹ́ bíi Olùtùnú, Afúniníyè & Ọ̀rẹ́.

Jesu fẹràn mi
Ọjọ́ Méje
Tí ẹnìkan bá béèrè lọ́wọ́ rẹ pé, “Kí nì mo ní láti gbàgbọ láti lè jẹ́ Kristẹni?” Kí nì ó sọ? Olùṣọ́-àgùntàn tó jẹ akọròyìn tẹ́lẹ̀ lo ọ̀rọ̀ orin, “Jésù Fẹ Mi Mo Mọ Bẹ́ẹ̀, Bíbélì L’o Sọ Fún Mi” láti jẹ́ kí ìgbàgbọ yé ọ. Akọ̀wé John S. Dickerson ṣàlàyé àwọn ìgbàgbọ ti Kristẹni àti ìdí tí wọ́n ṣe pàtàkì.