Ṣùgbọ́n, nínú àwọn ìlú ti àwọn orílẹ̀-èdè tí OLúWA Ọlọ́run rẹ ń fún ọ gẹ́gẹ́ bí ogún, má ṣe dá ohun ẹlẹ́mìí kankan sí. Pa wọ́n run pátápátá, àwọn ọmọ Hiti, ọmọ Amori, ọmọ Kenaani, ọmọ Peresi, ọmọ Hifi, ọmọ Jebusi gẹ́gẹ́ bí OLúWA Ọlọ́run rẹ ti pa á láṣẹ fún ọ.
Kà Deuteronomi 20
Feti si Deuteronomi 20
Pín
Fi gbogbo Èyá wéra: Deuteronomi 20:16-17
Ṣe àfipamọ́ àwọn ẹsẹ, kàá ní aìsìní orí ayélujára, wo àwọn àgékúrú ìkọ́ni, àti díẹ̀ síi!
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò