Deuteronomi 20:16-17

Deuteronomi 20:16-17 YCB

Ṣùgbọ́n, nínú àwọn ìlú ti àwọn orílẹ̀-èdè tí OLúWA Ọlọ́run rẹ ń fún ọ gẹ́gẹ́ bí ogún, má ṣe dá ohun ẹlẹ́mìí kankan sí. Pa wọ́n run pátápátá, àwọn ọmọ Hiti, ọmọ Amori, ọmọ Kenaani, ọmọ Peresi, ọmọ Hifi, ọmọ Jebusi gẹ́gẹ́ bí OLúWA Ọlọ́run rẹ ti pa á láṣẹ fún ọ.