1
Esekiẹli 22:30
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
“Èmi si wá ẹnìkan láàrín wọn, tí ìbá tún odi náà mọ́, tí ìbá dúró ní ibi tí ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, kí èmi má bá à parun: ṣùgbọ́n èmi kò rí ẹnìkan.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí Esekiẹli 22:30
2
Esekiẹli 22:31
Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi sí wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní OLúWA Olódùmarè wí.”
Ṣàwárí Esekiẹli 22:31
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò