1
2 Kronika 31:21
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Nínú ohun gbogbo tí ó dáwọ́lé ní ti iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Ọlọ́run àti ní ìgbọ́ràn sí òfin àti àwọn àṣẹ. Ó wá Ọlọ́run rẹ̀, ó sì ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn. Ó sì ṣe rere.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí 2 Kronika 31:21
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò