1
1 Ọba 11:4
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Bí Solomoni sì ti di arúgbó, àwọn ìyàwó rẹ̀ sì yí i ní ọkàn padà sí ọlọ́run mìíràn, ọkàn rẹ̀ kò sì ṣe déédé pẹ̀lú OLúWA Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọkàn Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe.
Ṣe Àfiwé
Ṣàwárí 1 Ọba 11:4
2
1 Ọba 11:9
OLúWA bínú sí Solomoni nítorí ọkàn rẹ̀ ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ OLúWA Ọlọ́run Israẹli, tí ó ti fi ara hàn án lẹ́ẹ̀méjì.
Ṣàwárí 1 Ọba 11:9
Ilé
Bíbélì
Àwon ètò
Àwon Fídíò