Àwọn ètò kíkà ọ̀fé àti àyọkà tó ní ṣe pẹ̀lú Luk 1:30

Awọn itan keresimesi
Ọjọ́ 5
Gbogbo ìtàn gidi ló ní ìyípadà ìtàn - àkókò àìròtẹ́lẹ̀ tí ó yí gbogbo nǹkan padà. Ọ̀kan lára àwọn ìyípadà ìtàn tó tóbi jùlọ nínú Bíbélì ni ìtàn Kérésìmesì. Ní ọjọ́ márùn-ún tó ń bọ̀, a máa ṣàwárí bí ìṣẹ̀lẹ̀ kan yìí ṣe yí ayé padà àti bí ó ṣe lè yí ayé rẹ padà lónìí.

Àṣàrò Nípa Kérésìmesì
Ọjọ́ Márùn-ún
Ìtàn Kérésìmesì wa bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìkéde áńgẹ́lì sí Màríà ó sì parí pẹ̀lú ìbẹ̀wò àwọn amòye. Nínú àwọn àṣàrò wọ̀nyí àti àwọn àmúlò ti ìtàn àkọsílẹ̀ Kérésìmesì èmi yóò tọ́ka sí ìwé Lúùkú púpọ̀, nítorí ìwé tirẹ̀ ni ó kún jùlọ nínú àwọn àkọsílẹ̀ ìhìnrere.

Jí Jókòó Níbi Ìdákẹ́ Rọ́rọ́: Ọjọ́ 7 Lórí Dí Dúró Sínú Ìlérí Ọlọ́run
Ọjọ́ Méje
Àwọn àkókò kan tí a gbá ìlérí Ọlọ́run mú, ṣùgbọ́n a kò rí ayé wa kí ó máa dọ́gba pẹ̀lú ìlérí náà tí Ọlọ́run fún wa. Ẹ̀wẹ̀ àkókò wà tí a bára wa ní oríta ní ìrìnàjò ayé wa, nígbàtí à ń gbára lé Ọlọ́run láti darí ipa ọ̀nà ayé wa, ṣùgbọ́n ìdákẹ́ rọ́rọ́ ni ohùn tó fọ̀ sí wa. Ètò ẹ̀kọ́ ọlọ́jọ́-7 yìí yóò sọ̀rọ̀ sí ọkàn rẹ nípa bí a ti ún rìn nínú ìfẹ́ Ọlọ́run nígbàtí ó dàbíi pé Ó dákẹ́ jẹ́.

KÉRÉSÌMESÌ: Ìmúṣẹ Ètò Ìdáǹdè Ọlọ́run
Ọjọ́ Mẹ́rìnlá
Àwọn òrìṣà èké tí àwọn ènìyàn mọ láti fi ṣe àpèjúwe òrìṣà kan tí wọ́n mọ̀ pé ó ní láti wà, kò ya'ni l'ẹ́nu pé, wọ́n jọ àwa ènìyàn gan-an. Wọ́n ní láti fi ìfọkànsìn mú wọn, kí wọ́n sì fún wọn ní rìbá kí wọ́n lè ṣe àkíyèsí wa. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tòótọ́ kan ṣoṣo náà ti gbé ìgbésẹ̀, ó sì ń wá wa kiri––láti gbà wá padà sí ọ̀dọ̀ ara rẹ̀. Èyí gan-an ni ìtàn Kérésìmesì.

Bíbọ̀wá: Ìrìn Àjò Sí Kérésìmesì
Ojó Mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
Ìtàn Kérésìmesì jẹ́ èyí tó ní ọlá jùlọ lóòótọ́: èyí tó dá lóríi ìṣòótọ́ Ọlọ́run, agbára, ìgbàlà, àti ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn. Jẹ́ kí a lọ lórí ìrìn àjò ọlọ́jọ́ mẹ́ẹ̀dọ́ńgbọ̀n láti ṣe àwárí ètò pípé Ọlọ́run láti gba ayé lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti àwọn ìlérí tí a mú wá sí ìmúṣẹ nípa ìbí Ọmọ Rẹ̀.