Eksodu 35:30-31
Eksodu 35:30-31 YCB
Nígbà náà ni Mose wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Wò ó, OLúWA ti yan Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ẹ̀yà Juda, Ó sì ti fi ẹ̀mí Ọlọ́run kún un, pẹ̀lú ọgbọ́n, òye, ìmọ̀ àti gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà
Nígbà náà ni Mose wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Wò ó, OLúWA ti yan Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ẹ̀yà Juda, Ó sì ti fi ẹ̀mí Ọlọ́run kún un, pẹ̀lú ọgbọ́n, òye, ìmọ̀ àti gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà