1
Saamu 126:5
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn yóò fi ayọ̀ ka.
Compare
Explore Saamu 126:5
2
Saamu 126:6
Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ, tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́, lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá, yóò sì ru ìtí rẹ̀.
Explore Saamu 126:6
3
Saamu 126:3
OLúWA ṣe ohun ńlá fún wa; nítorí náà àwa ń yọ̀.
Explore Saamu 126:3
Home
Bible
Plans
Videos