1
Esekiẹli 23:49
Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
Ìwọ yóò sì jìyà fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, ìwọ yóò sì gba àbájáde àwọn ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà tí o dá. Nígbà náà ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni OLúWA Olódùmarè.”
Compare
Explore Esekiẹli 23:49
2
Esekiẹli 23:35
“Nítorí náà báyìí ní OLúWA Olódùmarè wí: Níwọ́n bí ìwọ ti gbàgbé mi, tí ìwọ sì ti fi mi sí ẹ̀yìn rẹ, ìwọ gbọdọ̀ gba àbájáde ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti panṣágà rẹ.”
Explore Esekiẹli 23:35
Home
Bible
Plans
Videos